BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìbúgbàmù àdó olóró tó wáyé níbùdó àwọn ológun ní Mali, ohun tí a mọ̀ rèé
owurọ kutu ọjọ Abamẹta oni ni ibugbamu naa waye
Aiyedatiwa jẹ wá lówó oṣù mẹ́fa, ó tún fẹ́ lé wa níbi tí ìrandíran wa ń gbé láti 1943 - Àwọn àkàndá ẹ̀dá Ago Ireti figbeta l'Ondo
Yatọ si awon to ni arun ẹ̀tẹ̀ to n gbe ni Agọ ireti, awon mi-in naa n gbe nibẹ ti won ko ni arun yii ṣugbọn ti wọn ṣi jẹ akanda ti ẹya ara miran pe nija, pẹlu awọn to jẹ talika ti ko le da ọwọ mu lọ sẹnu rara.
Fídíò, Lisabi 2026: Wo bí àwọn ọmọ Abeokuta ṣe dábírà níbi ayẹyẹ ìrántí akọni wọn, Duration 2,01
Lasiko ti ogun Oyo n ja awon eeyan Ẹgba ni Lisabi ṣaaju ogun fun won, ni nnkan bii Senturi kejidinlogun si asiko yii, to si gba won lọwọ ijẹgaba awọn eeyan naa.
Ẹ má ṣe dojú ìjà kọ àwọn ọmọ onílùú lásìkò ìfẹ̀hónúhàn- Ìjọba Naijiria kìlọ̀ fáwon èèyàn rẹ̀ tó ń gbé ní South Africa
Ikilọ yii lo n waye lẹyin ti alakooso agba kan lati Naijiria fun Johannesburg, sọ pe iwadii fi han pe awon kan n pete iwọde tuntun lagbegbe Gauteng, laaarin ọjọ Aje si Ọjọruu oṣu yii (Monday 27 - Wednesday 29 April).
Ẹ gbà wá o, àwọn agbébọn ti fẹ́ pa wá tán - Àwọn ọ̀dọ́ Gúúsù Kwara figbeta
Nibi ti ọrọ naa ka wọn lara de, awọn ọdọ Guusu Kwara ti wọn n gbe niluu Eko, Ilorin ati awọn ilu mi-in tẹ ọkọ leti wa silẹ lati dara pọ mọ ifẹhonuhan yii.
Ohun tó fàá tí Ààrẹ Kenya fi sọ pé ọmọ Naijiria ò lè sọ èdè òyìnbó dáadáa
Ọrọ yii ti bẹyin yọ tori ọpọ ọmọ orilẹede Naijiria atawọn ọmọ orilẹede Afirika mii ni wọn ti bu ẹnu ẹtẹ lu Ruto wi pe o n tabuku orilẹede ilẹ Afirika mii.
Ìgbẹ́jọ́ ọmogun 36 tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé wọ́n fẹ́ dìtẹ̀ gbàjọba Tinubu bẹ̀rẹ̀ nílé ẹjọ́ iléeṣẹ́ ológun Naijiria
Olu ileeṣẹ ologun Naijiria to ṣe ifilọlẹ igbẹjọ naa lonii ọjọ Ẹti ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹrin yii sọ pe ẹsun iditẹ eyi to lewu fun aabo orilẹede lẹsun ti wọn fi kan awọn ọmogun naa.
Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ yá $516m láti ṣe ọ̀nà láti Sokoto sí Badagry
Ọrọ naa lo wa ninu lẹta kan ti Aarẹ igbimọ aṣofin naa, Godswill Akpabio ka niwaju awọn ọmọ ile.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,00
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Fídíò, Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan, Duration 4,29
Iyawo oloogbe sọ pe oun ati ọmọ oun sa asala fun ẹmi wọn ni awọn afurasi naa ko gbẹmi awọn naa.
Erin kọlu ìlú kan ní ìpínlẹ̀ Oyo, pa èèyàn kan, ẹlòmíì di àwátì
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Oyo, DSP Ayanlade Olayinka, fidi iṣẹlẹ naa mulẹ ninu atẹjade kan to fi lede.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ ìṣègùn OAU ṣubú lulẹ̀ lásìkò tó ń múra ìdánwò, jáde láyé
Iṣẹlẹ yii lo n waye lẹyin ti ọmọ ọdun mejidinlogun kan to n kẹkọọ imọ iṣẹgun nile ẹkọ kan naa, Timilehin Toromade jade laye loju orun rẹ lọjọ kẹfa, oṣu Kinni, ọdun 2026 yii.
Gbọin-gbọin ni a wà lẹ́yìn Makinde bí òkè, àhesọ ọ̀rọ̀ lásán n'ìròyìn tó ní a fẹ́ yọ ọ́ nípò – Ilé Aṣòfin Oyo
Adari ẹgbẹ oṣelu to pọju nile, Họnọrebu Sanjo Adedoyin, to n ṣoju ẹkun Guusu Ogbomoso lo dabaa wi pe ki ile dibo lati kede atilẹyin wọn fun Makinde.
Wo àwọn ilé tí ìjọba Eko kò fún láǹfàní láti lo iná 'Solar' láì gbàṣẹ àti ìgbésẹ̀ tó yẹ kí o gbé kí o tó ṣe é sílé rẹ
Ina Solar yii ti pọ kaakiri to bẹẹ ti wọn n lo o ni awọn igberiko kiri, ti ọpọ eeyan ko si duro de ina mọnamọna mọ.
Ṣé lóòótọ́ ni pé èèyàn mẹ́wàá tún ti lùgbàdì Covid-19 ní Naijiria? Ohun tí a mọ̀ rèé
Bakan naa ni awọn ẹka ilera kaakiri ipinlẹ Cross River naa ti sọ pe ko si akọsilẹ arun Corona mẹwaa lọdọ awọn.
Èèyàn 518 ló kú nínú rògbòdìyàn ètò ìdìbò Ààrẹ Tanzania – Ìwádìí
Igba akọkọ ree ti awọn alaṣẹ yoo mẹnuba iye eeyan to ku ninu ifẹhonuhan to waye lẹyin eto idibo naa.
Ọkùnrin tí ọlọ́pàá ká ẹ̀yà ara èèyàn mọ́ lọ́wọ́ l'Ondo dèrò àtìmọ́lé
Baba afurasri naa ti kọkọ fẹsun jiji alupupu Boxer Bajaj mẹta, ewurẹ mẹsan an, ẹrọ ilewọ Android mẹrin, epo pupa, silinda gaasi meji, atawọn nnkan mii kan an.
Mínísítà fọ́rọ̀ ohun àmúsagbára Adebayo Adelabu ṣàlàyé ìdí tó fi kọ̀wé fipò sílẹ̀
Adelabu ṣalaye igbesẹ rẹ ninu iwe kan to fi ranṣẹ si Aarẹ Bola Tinubu lọjọ kejilelogun oṣu kẹrin yii.
Ẹ wo bí ìgbẹ́jọ́ àwọn afurasí tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé wọ́n fẹ́ dìtẹ̀ gbàjọba Tinubu ṣe lọ l'Abuja
Gomina ipinlẹ Bayelsa tẹlẹ ri, Timipre Sylva, naa wa lara awọn afurasi ọhun, ṣugbọn nnkan ti a gbọ ni pe o ni na papa bora.
Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ sún ìdájọ́ ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn tí ADC àti PDP pè síwájú
Ko sẹni to le sọ igba ti ile ẹjọ to ga julọ yoo gbe idajọ rẹ kalẹ ọrọ yii, ọpọ lo si n kọminu tori idajọ naa niṣe pẹlu eto idibo ọdun 2027.
Ẹ foríjìn mí, mo ṣetán láti d'ówó padà f'áwọn tó bá fẹ́ gbowó tí wọ́n dá fún mi - Blessing CEO
Ti ẹ o ba gbagbe, Blessing ṣe fidio kan ninu eyi to ti bẹbẹ fun iranwọ owo lẹyin to ni oun ti lugbadi arun jẹjẹ, arun naa si ti de ipele ''stage 4.''
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí ọ̀gá ọlọ́pàá 167 fi ń sọ tẹnu wọn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣèbáwí ọlọ́pàá? Àlàyé rèé
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria, Anthony Placid, lo fọrọ yii lede loju opo ayelujara rẹ.
Tinubu yọ Mínísítà ètò ìṣúná Wale Edun nípò, fi Taiwo Oyedele rọ́pò rẹ̀
Gẹgẹ bi akọwe ijọba apapọ, George Akume, ti ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita ni irọlẹ ọjọ Iṣẹgun, minisita meji ni Aarẹ Tinubu yọ nipo ti o si ti rọpo wọn pẹlu.
Ìròyìn Pàtàkì
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Alága ìjọba ìbílẹ̀ Owo tí wọ́n já síhòhò l'Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé
Ṣaaju ni awọn asofin ijọba ibilẹ naa ti ni ki Tope Omolayo lọ rọ ọ kun nile foṣu mẹfa gbako, latari aawọ to ni pẹlu Ọlọwọ tilu ọwọ; Ọba Ajibade Ogunoye. Awọn ti ọrọ ijanisihoho naa soju wọn salaye, pe alaga yii pada sẹnu isẹ la
Irọ́ ni pé a ti dá ẹ̀yáwó tí à ń ṣe fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ dúró - NELFUND
Loju opo X ajọ NELFUND lo ti kede lọjọ Abamẹta to kọja, pe oun ko figba kankan gbe e jade pe oun dawọ ẹyawo duro na.
Bàbá kan yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ méje àti ọmọ ọlọ́mọ kan
Awọn ọlọpaa ibẹ ṣapejuwe ipaniyan naa bii "idaamu abele".
Wo nǹkan mẹ́tàdínlógún tí ìjọba ti fòfin dè pé wọn ò gbọdọ̀ kò wọlé sí Naijiria mọ́ látòkè òkun
Simẹnti, ọṣẹ, ajilẹ atawọn nnkan mi ti wa lara awọn ọja tawọn eeyan ko le ko wọle mọ bayii.
A ti yanjú aáwọ̀ láàárín Makinde àti Olubadan-Ìgbìmọ̀ ọmọ Ibadan
Atẹjade ni CCII fi sita lo kede eyi, Aarẹ wọn, Amofin Sulaimon Ajeniyi Ajewole si buwọ lu u.
APC kéde ₦100m bíi owó fọ́ọ̀mù ìdíje ipò ààrẹ, làwọn ọmọ Nàìjíríà bá pariwo
Fun awon oludije to fẹ dupo aarẹ ninu APC, ₦100 million ni won gbe e si pẹlu alaye pe ọgbọn miliọnu (30m) wa fun fifi ifẹ han lati dije, nigba ti aadọrin miliọnu (₦70 million) wa fun ifanikalẹ.
Amẹ́ríkà àti Iran ní ìjíròrò ń so èso rere àmọ́ kò tíì sí ìfẹnukò
Trump sọ fún àwọn akọ̀ròyìn ní ọjọ́ Àbámẹ́ta pé Iran ń ṣe bí wọ́n ṣe máa ń ṣe láti bíi ọdún mẹ́tàdínláàádọ́ta sẹ́yìn.
Ṣé lóòótọ́ ni pé ìdìbó 2027 tó ń bọ̀ ló jẹ́ kí ètò ààbò mẹ́hẹ ní Naijiria? Ohun tí a mọ̀ rèé
Nigba to n ṣalaye ajọṣepọ to wa laaarin eto aabo ati idibo, Ọmọwe Kabiru Adamu, oludasilẹ ileeṣẹ eto aabo Beacon Security sọ pe iwadii ti fi han pe ajọṣepọ wa laaarin aabo ati idibo loootọ.










































































