BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
04:32
Fídíò,
'Ibi alálàájì tó gẹṣin lọ Jumat lọmọ mi lọ tí wọ́n fi jíi gbé, bí mo ṣe ríi lẹ́yìn ọdún kan àti oṣù méjì rèé'
, Duration4,32
05:02
Fídíò,
Àwọn kan fẹ́ kí n sọ ₦25 milíọ̀nù tí Ogogo tọ́jú sọ́wọ́ mi di owó Mọ́ṣáláṣí ṣùgbọ́n mo ní rárá – Ìmáàmù ìlú Ilaro
, Duration5,02
05:33
Fídíò,
Tírélà ló pa ọkọ mi tó jẹ́ awakọ̀ èrò, ìdá mẹ́ta ẹ̀bùn owó ló kàn mì, ìyá ọkọ mi kò bèèrè àwọn ọmọ di ìsinyìí - Opó
, Duration5,33
02:29
Fídíò,
Irọ́ ni Portable n pa wí pé mo gé òun jẹ, ohun tó ṣẹlẹ̀ lásìkò ìjà wa rèé - Charles Okocha
, Duration2,29
02:46
Fídíò,
Wo pàtàkì òrìṣà Vodu Dangbe, níbi táwọn olùjọ́sìn ti ń gbé ejò sọ́rùn, kẹ̀yìn sí ìbálòpọ̀, jíjẹ epo tàbí iyọ̀ ṣaájú ètùtù
, Duration2,46
02:20
Fídíò,
Ìfẹ́ tí Ajá mi fi hàn sí mi, ló gba ẹ̀mí mi là lásìkò tí mo fẹ́ pa ara mi - Oreoluwa Osoba
, Duration2,20
05:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration5,13
03:37
Fídíò,
Ǹjẹ́ ó tọ́ kí òbí máa kàn án ní dandan f'áwọn ọmọ láti tọ́jú wọn lọ́jọ́ ogbó?
, Duration3,37
05:53
Fídíò,
Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan
, Duration5,53
02:30
Fídíò,
Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa
, Duration2,30
02:54
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé
, Duration2,54
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration4,02
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
'Ọ̀nà wà láti ìlú wa lọ sí ọ̀run, egúngún kò sì gbọdọ̀ wọ ìnú ìlú wa'- Èyí ni ìlú tí a kò tí gbọ́dọ̀ ṣe ògùn owó tàbí sun àgbàdo tà
wákàtí 2 sẹ́yìn
Ṣé òótọ́ ni pé àgbo jẹ̀dí tí wọ́n fi ògógóró pò ló gbẹ̀mí ọ̀gọ̀rọ̀ èèyàn l'Ondo?
ìṣẹ́jú 56 sẹ́yìn
APC fagilé ẹjọ́ tí wọ́n pè tako èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ́ Osun tó gbé Adeleke wọlé fún sáà kejì
wákàtí kan sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Àṣírí gbọ́mọgbọ́mọ méjì tó ń wọ Hijab láì ṣe Mùsùlùmí tú lásìkò tí wọn tún fẹ́ jí ọmọ míì gbé
5 Owewe 2026
Ìjọba Eko fèsì sí ẹ̀sùn tí obìnrin kan fi kan ilé ìwòsàn Randle nínú fídíò tó gba orí ayélujára
5 Owewe 2026
NRC àti NSCDC dá ìgbìyànjú fífọ́ àti jíjí ohun èlò ojú irin dúró l'Osun
5 Owewe 2026
Wo ipa tí mímú àlékún bá iye owó lílẹ pátákó ìpolongo ìbò máa ní lórí ètò ìdìbò 2027
5 Owewe 2026
Ìjọba Plateau gbé gbogbo ilé ẹ̀kọ́ tì pa nítorí àrùn Diphtheria tó búrẹ́kẹ níbẹ̀
5 Owewe 2026
Gani Fawehinmi: Agbẹjọ́rò àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọniyàn ni Nàìjíríà ti ọ̀rọ̀ tálákà jẹ lógún
5 Owewe 2026
Kí ló fa ikú pásítọ̀ ìjọ Celestial kan àti ìyàwó rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n jà tán? Àlàyé rèé
3 Owewe 2026
Kí ló dé tí ẹnu ń kun Sarafadeen Alli, olùdíje sípò gómìnà l'Oyo, torí fọ́nrán ibi tó ti gbé akẹ́kọ̀ọ́-kùnrin kan sórí ẹsẹ̀?
3 Owewe 2026
Kí ló mú Arsenal lulẹ̀ pẹ̀lú èròngbà rẹ̀ láti ra Osimhen àti Alvarez wá sí Premier League? Ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé
2 Owewe 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ìṣẹ́ alájótà, àtàwọn ohun tuntun míràn tí o kò mọ̀ nípa Temitope Osoba, gbajúmọ̀ òṣèré tí wọ́n ń sin òkú rẹ̀ lónìí
2
Kò sí orúkọ Oriyomi Hamzat tàbí Gudugudu gẹ́gẹ́bí olùdíje sípò Gómìnà fẹ́gbẹ́ Accord nínú àkọsílẹ̀ INEC ní ìpínlẹ̀ Oyo - Ìwádìí BBC
3
Kí ló dé tí iléeṣẹ́ ọmọogun fi gbé adarí ikọ̀ tó ń gbógun ti Boko Haram àtàwọn agbébọn kúrò pẹ̀lú àwọn ọ̀gágun 15 míràn? Ohun tí a mọ̀ rèé
4
Ó tó gẹ́! A ò fẹ́ kí Sẹ́nẹ́tọ̀ Francis Fadahunsi ṣojú wa mọ́ nílé aṣòfin àgbà l'Abuja, - Àwọn Ọ̀dọ́ Ilẹ̀ Ijesa yari
5
Kí ló ṣokùnfà ikú gbajúmọ̀ òṣèrèbìnrin, Nimmy Ferrari tó jáde láyé lásìkò tó ń palẹ̀mọ́ láti ṣí ilé tuntun tó kọ́?
6
Wo bí ètò ìsínkú gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, Temitope Osoba tó jáde láyé láìpẹ́ yìí yóò ṣe lọ
7
'Mo wá sí Naijiria láti kojú ọmọ Yahoo tó fẹ́ lu ìyá mi ni jìbìtì àmọ́ ohun tí mo bábọ̀ rèé'
8
Ọbalayé tó kéré jùlọ lágbáyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 34
9
APC fagilé ẹjọ́ tí wọ́n pè tako èsì ìdìbò gómìnà ìpínlẹ́ Osun tó gbé Adeleke wọlé fún sáà kejì
10
Ǹjẹ́ o mọ̀ pé àwọn èèyàn kan wà tí wọn kò ní ilà ọwọ́? Ohun tó fà á ree
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology